< Jeremijas 2 >

1 Un Tā Kunga vārds uz mani notika un sacīja:
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
2 Ej un sauc Jeruzālemes ausīs un saki: Tā saka Tas Kungs: Es tevi pieminēju, kad tu vēl biji mīlīga meita un mīļa brūte, kad tu Man staigāji pakaļ tuksnesī, neapsētā zemē.
“Lọ kí o sì kéde sí etí Jerusalẹmu pé: “Báyìí ni Olúwa wí, “‘Èmi rántí ìṣeun ìgbà èwe rẹ, ìfẹ́ ìgbéyàwó rẹ àti nígbà tí ìwọ tẹ̀lé mi nínú ijù, nínú ìyàngbẹ ilẹ̀.
3 Israēls bija Tam Kungam svētīts un viņa augļu pirmaji; visi, kas to ēda, tie tapa noziedzīgi, ļaunums nāca pār tiem, saka Tas Kungs.
Israẹli jẹ́ mímọ́ sí Olúwa, àkọ́kọ́ èso ìkórè rẹ̀, gbogbo ẹnikẹ́ni tí ó jẹ run ni a ó dá lẹ́bi, ibi yóò sì wá sí orí wọn,’” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí.
4 Klausiet Tā Kunga vārdu, Jēkaba nams, visas Israēla nama ciltis.
Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ìdílé Jakọbu àti gbogbo ẹ̀yin ará ilé Israẹli.
5 Tā saka Tas Kungs: kādu netaisnību jūsu tēvi pie Manis atraduši, ka tie tālu no Manis atkāpušies un nelietībai dzinušies pakaļ un tapuši nelieši,
Báyìí ni Olúwa wí: “Irú àìṣedéédéé wo ni baba yín rí lọ́wọ́ mi, tí wọ́n fi jìnnà sí mi? Wọ́n tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán, àwọn fúnra wọn sì di asán.
6 Un nav sacījuši: kur ir Tas Kungs, kas mūs izveda no Ēģiptes zemes, kas mūs vadīja tuksnesī, tukšā un nestaigātā zemē, izkaltušā un nāves ēnas zemē, tai zemē, kur neviens negāja cauri un kur neviens cilvēks nedzīvoja?
Wọn kò béèrè, ‘Níbo ni Olúwa wà, tí ó mú wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, tí ó mú wa la aginjù já, tí ó mú wa la àárín pẹ̀tẹ́lẹ̀ àti ihò, ìyàngbẹ ilẹ̀ àti òkùnkùn biribiri, ilẹ̀ ibi tí ẹnikẹ́ni kò là kọjá, tí ẹnikẹ́ni kò sì tẹ̀dó sí?’
7 Un Es jūs ievedu auglīgā zemē, ēst viņas augļus un viņas labumu. Bet kad jūs nācāt iekšā, tad jūs Manu zemi sagānījāt un darījāt Manu īpašumu par negantību.
Èmi mú yín wá sí ilẹ̀ ọlọ́ràá láti máa jẹ èso ibẹ̀ àti ọrọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin wọ inú rẹ̀, ẹ sì bà á jẹ́, ẹ sì sọ ogún mi di ohun ìríra.
8 Priesteri nesacīja: kur ir Tas Kungs? Un bauslības mācītāji Mani nepazina un gani atkāpās no Manis, un pravieši mācīja Baāla vārdā un dzinās pakaļ tiem, kas nekā neder.
Àwọn àlùfáà kò béèrè wí pé, ‘Níbo ni Olúwa wà?’ Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú òfin kò si mọ̀ mí, àwọn olùṣọ́ sì ṣẹ̀ sí mi. Àwọn wòlíì sì ń sọtẹ́lẹ̀ nípa òrìṣà Baali, wọ́n sì ń tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán.
9 Tāpēc Es vēl ar jums tiesāšos, saka Tas Kungs, un ar jūsu bērnu bērniem Es tiesāšos.
“Nítorí náà, mo fi ẹ̀sùn kàn yín lẹ́ẹ̀kan sí i,” ni Olúwa wí. “Èmi ó sì fi ẹ̀sùn kan àwọn ọmọ ọwọ́ rẹ.
10 Jo ceļaties pāri uz Ķitiju salām un lūkojiet un sūtiet uz Ķedaru un ņemiet labi vērā un raugiet, vai tur tā noticis.
Rékọjá lọ sí erékùṣù àwọn ara Kittimu, kí ẹ sì wò ó, ránṣẹ́ lọ sí ìlú Kedari, kí ẹ sì kíyèsi gidigidi; kí ẹ wò bí irú nǹkan báyìí bá ń bẹ níbẹ̀?
11 Vai kādi pagāni dievus pārmijuši, jebšu tie nav dievi? Bet Mani ļaudis savu godību pārmijuši ar to, kas nekā neder.
Orílẹ̀-èdè kan ha á pa ọlọ́run rẹ̀ dà? (Síbẹ̀, wọ́n kì í ṣe iṣẹ́ ọlọ́run.) Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi ti pààrọ̀ Ọlọ́run ògo wọn fún àwọn ère tí kò níyì.
12 Iztrūcinājaties par to, debesis, un trīciet un drebiet ļoti, saka Tas Kungs.
Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì kí ẹ sì wárìrì pẹ̀lú ìbẹ̀rù ńlá,” ni Olúwa wí.
13 Jo Mani ļaudis dara divkārtīgu ļaunumu: tie Mani atstāj, to dzīvo ūdens avotu, un izcērt sev akas, cauras akas, kas ūdeni netur.
“Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì, wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, Èmi orísun omi ìyè, wọ́n sì ti ṣe àmù, àmù fífọ́ tí kò lè gba omi dúró.
14 Vai Israēls ir kalps jeb dzimts vergs? Kāpēc tad viņš ir palicis par laupījumu?
Israẹli ha á jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ ẹrú nípa ìbí? Kí ló ha a dé tí ó fi di ìkógun?
15 Jaunie lauvas rūc pret viņu, tie paceļ savas balsis un posta viņa zemi; viņa pilsētas ir sadedzinātas, ka neviens tur nedzīvo.
Àwọn kìnnìún ké ramúramù; wọ́n sì ń bú mọ́ wọn. Wọ́n ti fi ilẹ̀ rẹ̀ ṣòfò; ìlú rẹ̀ ti di jíjóná, ó sì ti di ìkọ̀sílẹ̀.
16 Arī Nofas un Takvanesas bērni tev nogana galvu.
Bákan náà, àwọn ọkùnrin Memfisi àti Tafanesi wọ́n ti fa adé orí rẹ yọ.
17 Vai tu pats sev to nedari, ka tu To Kungu, savu Dievu atstāji tanī laikā, kad Viņš tevi veda uz ceļu?
Ẹ̀yin kò ha a ti fa èyí sórí ara yín nípa kíkọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀ nígbà tí ó tọ́ ọ lójú ọ̀nà?
18 Un nu, ko tev iet Ēģiptes ceļu, dzert Šihora ūdeni? Un ko tev iet Asura ceļu, dzert lielās upes ūdeni?
Kí ló dé tí o ṣe wá lọ Ejibiti láti lọ mu omi ní Ṣihori? Kí ló dé tí o sì fi lọ sí Asiria láti lọ mú omi ni odò Eufurate náà?
19 Tava blēdība tevi pārmācīs, un tava atkāpšanās tevi sodīs. Tāpēc atzīsti un redzi, ka tas ir ļauni un rūgti, ka tu To Kungu, savu Dievu, atstāji, un Manas bijāšanas nav pie tevis, saka Tas Kungs Dievs Cebaot.
Iṣẹ́ búburú yín yóò fìyà jẹ yín ìpadàsẹ́yìn rẹ yóò sì bá ọ wí mọ̀ kí o sì rí i wí pé ibi àti ohun búburú yóò sì jẹ́ tìrẹ nígbà tí o ti kọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀, ẹ kò sì ní ìbẹ̀rù fún mi,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
20 Jo no veciem laikiem tu savu jūgu esi salauzusi un savas saites saraustījusi un saki: es nekalpošu; jo uz visiem augstiem pakalniem un apakš visiem zaļiem kokiem tu skraidīji, maucību dzīt.
“Nígbà àtijọ́, o ti fọ́ àjàgà rẹ sọnù, ìwọ sì já ìdè rẹ; ìwọ wí pé, ‘Èmi kì yóò sìn ọ́!’ Lóòtítọ́, lórí gbogbo òkè gíga ni àti lábẹ́ igi tí ó tànkálẹ̀ ni ìwọ dùbúlẹ̀ sí gẹ́gẹ́ bí panṣágà.
21 Es tevi biju dēstījis par jauku vīna koku, par it taisnu sēklu; kā tad tu Man esi pārvērtusies par sveša vīna koka rūgto meža zaru?
Èmi ti gbìn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àjàrà ọ̀tọ̀, gẹ́gẹ́ bí ìṣúra ọlọ́lá. Báwo wá ni ìwọ ṣe yípadà sí mi di àjàrà búburú àti aláìmọ́?
22 Jo jebšu tu mazgātos ar sārmu un ņemtu daudz ziepes klāt, tomēr tavs noziegums paliek iezīmēts manā priekšā, saka Tas Kungs Dievs.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o wẹ ara rẹ pẹ̀lú sódà tí o sì lo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọṣẹ síbẹ̀síbẹ̀ èérí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ níwájú,” ni Olúwa Olódùmarè wí.
23 Kā tu vari sacīt, es neesmu sagānījusies, es Baāliem neesmu dzinusies pakaļ? Redzi savu ceļu tai ielejā, ņem vērā, ko tu esi darījusi,
“Báwo ni ìwọ ṣe wí pé, ‘Èmi kò ṣe aláìmọ́, Èmi kò sá à tẹ̀lé àwọn Baali’? Wo bí o ṣe hùwà ní àfonífojì; wo ohun tí o ṣe. Ìwọ jẹ́ abo ìbákasẹ tí ń sá síyìn-ín sọ́hùn-ún.
24 Tu čaklā kamieļu māte, kas šurpu turpu skraida, meža ēzeļu māte, ar tuksnesi apradusi, kas savā kārībā elš, - kas viņas karstumu savaldīs? Kas to grib meklēt tam nav jāpiekūst; jaunā mēnesī to var atrast.
Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí ń gbé aginjù tí ń fa ẹ̀fúùfù ìfẹ́ sí i mu rẹ, ta ni ó le è mú dúró ní àkókò rẹ̀? Kí gbogbo àwọn akọ ẹran tí o wá a kiri kì ó má ṣe dá ara wọn lágara, nítorí wọn yóò rí ní àkókò oṣù rẹ̀.
25 Neskrej tā, ka tev apavi nokrīt un ka tu noslāpsti. Bet tu saki: tas ir velti, nekā! Jo es mīlēju tos svešos un dzīšos tiem pakaļ.
Dá ẹsẹ̀ dúró láìwọ bàtà, àti ọ̀fun rẹ nínú òǹgbẹ. Ṣùgbọ́n ìwọ wí pé, ‘Asán ni! Èmi fẹ́ràn àwọn ọlọ́run àjèjì, àwọn ni èmi yóò tọ̀ lẹ́yìn.’
26 Tā kā zaglis kaunas, kad to pienāk, tā Israēla nams taps kaunā, paši, viņu ķēniņi, viņu lielkungi un viņu priesteri un viņu pravieši,
“Gẹ́gẹ́ bí a ṣe ń dójútì olè nígbà tí a bá mú u, bẹ́ẹ̀ náà ni ojú yóò ti ilé Israẹli— àwọn ọba àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn àlùfáà àti wòlíì wọn pẹ̀lú.
27 Kas uz koku saka: tu esi mans tēvs, - un uz akmeni: tu mani esi dzemdinājis. Jo tie Man piegriež muguru, ne vaigu. Bet nelaimes dienā tie saka: celies un izpestī mūs.
Wọ́n sọ fún igi pé, ‘Ìwọ ni baba mi,’ àti sí òkúta wí pé, ‘Ìwọ ni ó bí mi,’ wọ́n ti kọ ẹ̀yìn wọn sí mi, wọn kò kọ ojú sí mi síbẹ̀ nígbà tí wọ́n bá wà nínú ìṣòro, wọn yóò wí pé, ‘Wá kí o sì gbà wá!’
28 Kur tad ir tavi dievi, ko tu sev esi taisījusi? Lai tie ceļas, vai tie bēdu laikā tevi var izpestīt; jo cik tev pilsētu, tik tev arī dievu, Jūda!
Níbo wá ni àwọn ọlọ́run tí ẹ ṣe fúnra yín ha a wà? Jẹ́ kí wọ́n wá kí wọ́n sì gbà yín nígbà tí ẹ bá wà nínú ìṣòro! Nítorí pé ẹ̀yin ní àwọn ọlọ́run púpọ̀, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ni àwọn ìlú, ìwọ Juda.
29 Kāpēc jūs strīdaties pret Mani? Jūs visi no Manis esat atkāpušies, saka Tas Kungs.
“Kí ló dé tí o ṣe wá ń fi ẹ̀sùn kàn mí? Gbogbo yín ni ó ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi,” ni Olúwa wí.
30 Jūsu bērnus Es esmu velti sitis, tie to pārmācību nav pieņēmuši. Jūsu zobens ir aprijis jūsu praviešus, kā plēsīgs lauva.
“Nínú asán mo fìyà jẹ àwọn ènìyàn yín, wọn kò sì gba ìbáwí. Idà yín ti pa àwọn wòlíì yín run, gẹ́gẹ́ bí kìnnìún tí ń bú ramúramù.
31 Ak tu tauta, ņem jel vērā Tā Kunga vārdu! Vai tad Es Israēlim esmu tuksnesis vai tumša zeme? Kāpēc tad Mani ļaudis saka: mēs iesim savā vaļā, mēs nenāksim vairs pie Tevis?
“Ẹ̀yin ìran yìí, ẹ kíyèsi ọ̀rọ̀ Olúwa: “Mo ha ti di aginjù sí Israẹli tàbí mo jẹ ilẹ̀ olókùnkùn biribiri? Èéṣe tí àwọn ènìyàn mi ṣe wí pé, ‘A ní àǹfààní láti máa rìn kiri; àwa kì yóò tọ̀ ọ́ wá mọ́?’
32 Vai jaunava aizmirst savu rotu, vai brūte savu greznumu? Bet Mani ļaudis Mani ir aizmirsuši jau neskaitāmas dienas.
Wúńdíá ha le gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀, tàbí ìyàwó ohun ọ̀ṣọ́ ìgbéyàwó rẹ̀? Síbẹ̀, àwọn ènìyàn mi ti gbàgbé mi ní ọjọ́ àìníye.
33 Cik brangi tavi ceļi, meklēt mīlestību! Tāpēc tu arī radini savus ceļus uz blēdībām.
Ìwọ ti jẹ́ ọlọ́gbọ́n tó nípa ọ̀rọ̀ ìfẹ́! Àwọn obìnrin búburú yóò kẹ́kọ̀ọ́ nípa ọ̀nà rẹ.
34 Pat pie tavu drēbju vīlēm atrodas nabagu nenoziedzīgu dvēseļu asinis, ko tu nepienāci kā ielauzušos. Bet par to visu (Es ar tevi tiesāšos).
Lórí aṣọ rẹ ni wọ́n bá ẹ̀jẹ̀ àwọn tálákà aláìṣẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò ká wọn mọ́ níbi tí wọ́n ti ń rùn wọlé. Síbẹ̀ nínú gbogbo èyí
35 Un tu saki: es esmu nenoziedzīga, tāpēc lai viņa bardzība no manis nogriežas. Redzi, Es par to tiesāšos ar tevi, ka tu saki: es neesmu grēkojusi!
ìwọ sọ wí pé, ‘Èmi jẹ́ aláìṣẹ̀; kò sì bínú sí mi.’ Èmi yóò mú ìdájọ́ mi wá sórí rẹ nítorí pé ìwọ wí pé, ‘Èmi kò dẹ́ṣẹ̀.’
36 Kam tu tik ļoti steidzies pārgrozīt savu ceļu? Pie Ēģiptes tu tāpat paliksi kaunā, ka tu kaunā palikusi pie Asura.
Èéṣe tí ìwọ fi ń lọ káàkiri láti yí ọ̀nà rẹ padà? Ejibiti yóò dójútì ọ́ gẹ́gẹ́ bí i ti Asiria.
37 Arī no turienes tu iziesi, rokas pār galvu sasizdama. Jo Tas Kungs ir atmetis, uz ko paļaujies, un tev ar viņiem labi neizdosies.
Ìwọ yóò sì fi ibẹ̀ sílẹ̀ pẹ̀lú kíkáwọ́ rẹ lé orí rẹ, nítorí pé Olúwa ti kọ̀ àwọn tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé sílẹ̀, kì yóò sí ìrànlọ́wọ́ kankan fún ọ láti ọ̀dọ̀ wọn.

< Jeremijas 2 >