< Genesis 14 >

1 Ní àsìkò yìí ni Amrafeli ọba Ṣinari, Arioku ọba Ellasari, Kedorlaomeri ọba Elamu àti Tidali ọba Goyimu
Ana knafina ana mopafima nemaniza kini vahe'mo'zara ha' hu'naze. Mago kaziga mani'naza kini vahe'mokizmi zamagi'a, Amrafeli'a Babiloni kumate kini nere. Arioki'a Elasa kumate kini nere. Kedolaoma'a Elami kumate kini nere. Tidali'a Goimi kumate kini nere.
2 jáde lọ láti bá Bera ọba Sodomu, Birṣa ọba Gomorra, Ṣenabu ọba Adma, Ṣemeberi ọba Seboimu àti ọba Bela (èyí ni Soari) jagun.
Hagi vu'za ha' ome huzmante'nazana Bera'a Sodomu kumateti kini nere. Birsa'a Gomora kumateti kini nere. Sinabu'a Adma kumateti kini nere. Semeba'a Zeboimi kumate kini nere. Hagi Bela kumaku'ma, Zoari kumarema nehaza kumateti kini ne'ene hara hu'naku hu'naze.
3 Gbogbo àwọn ọba wọ̀nyí ni ó kó ogun wọn jọ pọ̀ sí àfonífojì Siddimu (ti o túmọ̀ sí Òkun Iyọ̀).
Hagi ana knafina e'i ana kumatera kini vahe'mo'za magopi hagerafi'za Sidimi krahopi nemani'zane. Ana kazigagura menina Fri Hagerine hu'za nehaze.
4 Fún ọdún méjìlá gbáko ni wọ́n ti ń sin Kedorlaomeri bí ẹrú. Ṣùgbọ́n nígbà tí ó di ọdún kẹtàlá wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí i.
E'i ana kumatamimpi vahera 12fu'a zagegafufina Kedolaoma kegava huzmantege'za mani'naze. Hagi 13nima hiankafufina zamasi vazige'za, ke'a antahi omi'naze.
5 Ní ọdún kẹrìnlá, ni Kedorlaomeri àti àwọn ọba tí wọ́n ti jọ ni májẹ̀mú àṣepọ̀ wá, wọ́n ṣígun, wọ́n sì ṣẹ́gun ará Refaimu ní Aṣteroti-Karnaimu, àwọn ará Susimu ni Hamu, àwọn ará Emimu ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Kiriataimu,
Hagi 14nima hiankafufina Kedalaoma'ene hagerafi'za mani'naza kini vahe'mo'za eza Refaim vahe'ma, Astero-Karnaimi kumate'ene Zuzimi kumate'ene Hami kumate'ene, Emimi kumate'ene Save-Kiriataim kumate vahe'ene,
6 àti àwọn ará Hori ní orí òkè wọ̀n-ọn-nì Seiri, títí ó fi dé Eli-Parani ní etí ijù.
Horaeti kumate vahe'enena ha' eme huzmanteza zamavaririge'za Idomu mopa zamirega El-parani nevazage'za, zamarotgo hu'za hagege hu'nea ka'ma mopa me'nea tvaonte vu'naze.
7 Wọ́n sì tún yípadà lọ sí En-Miṣpati (ti o túmọ̀ sí Kadeṣi), wọ́n sì ṣẹ́gun gbogbo ilẹ̀ àwọn Amaleki, àti àwọn ará Amori tí ó tẹ̀dó sí Hasason Tamari pẹ̀lú.
Hagi ete rukrahe'ma hu'za En-mispatima ne-e'za, Amori vahe mopa zamahe'za nehanare'za, Hazazon-tamari nemaniza, Amori vahe'mokizmi mopanena ha' huzmante'za eri'naze.
8 Nígbà náà ni ọba Sodomu, ọba Gomorra, ọba Adma, ọba Seboimu àti ọba Bela (èyí ni Soari), kó àwọn ọmọ-ogun wọn, wọ́n sì pa ibùdó ogun wọn sí Àfonífojì Siddimu,
Anantera Sodomu kinigi, Gomora kinigi, Adma kinigi, Zeboim kinigi, Bela kiniki, Belagura menina Zoari hu'za nehazankino, ana 5fu'a kini vahe'mo'za eri mago hute'za, Sidim agupofi hara hunaku tro hu'naze. (Dead Sea)
9 láti kojú ìjà sí Kedorlaomeri ọba Elamu, Tidali ọba Goyimu, Amrafeli ọba Ṣinari àti Arioku ọba Ellasari (ọba mẹ́rin kọjú ìjà sí ọba márùn-ún).
Hagi Sidim agupofima ha'ma hazana, Kedolaoma'a Elami kini neki, Tidali'a Goimi kini neki, Amrafeli'a Sainari kinigi, Arioku'a Elasari kini ne'ki hu'za ana 4'a kini vahe'mo'za 5fu'a kini vahe'ene Fri Hagerima me'nea agupofi hara hu'naze.
10 Àfonífojì Siddimu sì kún fún kòtò ọ̀dà ilẹ̀, nígbà tí ọba Sodomu àti ọba Gomorra sì sá, díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin ogun náà ṣubú sínú àwọn kòtò náà, àwọn tókù sì sálọ sì orí òkè.
Ana agupofina koltama kafizama eneri'za keriramina hakare'a me'neankino, Sodomu kini ne-ene Gomora kini ne'ene sondia vahe'znine koro freza ne'eza ana keriramimpi tamizageno, mago'a amanema mani'zamo'za fre'za agonarega vu'naze.
11 Àwọn ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin náà sì kó gbogbo ẹrù Sodomu àti Gomorra àti oúnjẹ wọn; wọ́n sì lọ.
Ha'ma hugateraza 4'a kini vahetamine sondia vahe'zmimo'za, Sodomu kumateti'ene Gomora kumatetira maka fenozmine hozafinti mika ne'zazminena eri'za vu'naze.
12 Wọ́n sì mú Lọti ọmọ arákùnrin Abramu tí ń gbé ní Sodomu àti gbogbo ohun ìní rẹ̀.
Ana nehu'za Abramuna nefu mofavre Loti'a Sodomu kumate mani'nege'za nevre'za, afufenoma'ane eri'za vu'naze.
13 Ẹnìkan tí ó sá àsálà sì wá ròyìn fún Abramu, ará Heberu ni. Abramu sá ti tẹ̀dó sí ẹ̀gbẹ́ igi ńlá igbó Mamre ará Amori, arákùnrin Eṣkolu àti Aneri: àwọn ẹni tí ó ń bá Abramu ní àṣepọ̀.
Hianagi anampinti mago ne'mo zamatreno freno nevuno, Hibru ne' Abramuna ana mikozamofo nenekea ome asmi'ne. Ana knafina Abramu'a Amori ne' Mamre oki zafa agafare mani'ne. Hagi Mamre'a Eskoline, Anelkizni'a neznafukino Abramu'ene tragote'za mani'nazageno anara hu'ne.
14 Nígbà tí Abramu gbọ́ wí pé, a di Lọti ní ìgbèkùn, ó kó àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ tí a bí sí ilẹ̀ rẹ̀ tí ó sì ti kọ́ ni ogun jíjà jáde, wọ́n jẹ́ okòó lé lọ́ọ̀dúnrún ó dín méjì ènìyàn, ó sì lépa wọn títí dé Dani.
Hagi ha' vahe'mo'zama Lotima avre'za vu'naza nanekema Abramu'ma nentahino'a, agranema maninaza vahe'mo'zakasezmante'za ha'zama rempi huzamige'za antahi'naza vahetamina 318ni'a vahe zamavare'za zamarotgo hu'za vuvava hu'za Dani uhanati'naze.
15 Ní ọ̀gànjọ́ òru, Abramu pín àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ sí méjì, ó sì kọlù wọ́n, ó sì ṣẹ́gun wọn, ó sì lé wọn títí dé Hoba tí ó wà ní apá òsì Damasku.
Abramu'a eri'za vahe'a ana kenage zamazeri atru huno tarefi refko huzmantege'za nevu'za, ha' vahera hara hu zamagatere'za zamarotgo hu'za Damaskas kumamofo noti kaziga Hoba uhanati'naze.
16 Gbogbo ìkógun ni ó rí gbà padà àti ọmọ arákùnrin rẹ̀, Lọti pẹ̀lú ohun ìní rẹ̀, àti àwọn obìnrin pẹ̀lú àwọn ènìyàn tókù.
Hagi ha'ma eme hu'za maka fenone, negana mofavre Lotine, maka'zane a'nene vahe'ene hapinti eri'za vu'naza zanena Abramu'a mika zana ete erino ene.
17 Nígbà tí Abramu ti ṣẹ́gun Kedorlaomeri àti àwọn ọba tí ó pẹ̀lú rẹ̀, ọba Sodomu lọ pàdé rẹ̀ ní àfonífojì Ṣafe (èyí ni àfonífojì Ọba).
Anantera Abramu'a Kedalaoma'ene mani'naza kini vahe ha' huzmagatereteno ete e'ne. Hanki Sodomu kini ne'mo'a Save agupofi eme agenaku e'ne. Ana agupogura kini vahe'mokizmi agupoe hu'za nehaze.
18 Melkisedeki ọba Salẹmu sì mú oúnjẹ àti ọtí wáìnì jáde wá. Òun ni àlùfáà Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo.
Melkizedeki'a Salemi kinigino, bretine, wainine erino eme ami'ne, agra Marerisa Anumzamofo pristi nere.
19 Ó sì súre fún Abramu, wí pé, “Ìbùkún ni fún Abramu ti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo, Ẹni tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Abramuna amanage huno asomu kea hunte'ne, Monane mopane eri fore hu'nea Marerisa Anumzamo'a kagrira asomura hugantegahie.
20 Ìbùkún sì ni fún Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo jùlọ, tí ó fi àwọn ọ̀tá rẹ lé ọ lọ́wọ́.” Abramu sì fún un ní ìdámẹ́wàá ohun gbogbo.
Ha' vahe ka'a kagri kazampima ante'nere Marerisa Anumzamofo ra agi amisune. Higeno Abramu'a mika zama eri'nefintira refko huno 10ni'a kevu anteteno, anampinti mago kevu Melkizedekina ami'ne.
21 Ọba Sodomu sì wí fún Abramu pé, “Kó àwọn ènìyàn mi fún mi, ṣùgbọ́n mú àwọn ẹrù fún ara rẹ.”
Sodomu kini ne'mo'a Abramunkura amanage hu'ne, mika vahe'zaga nagri nenaminka, Mika fenona kagraka'a erio.
22 Ṣùgbọ́n Abramu dá ọba Sodomu lóhùn pé, “Mo ti búra fún Olúwa, Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo, tí ó dá ọ̀run àti ayé, mo sì ti gbọ́wọ́ sókè,
Hianagi Abramu'a Sodomu kini nekura amanage hu'ne, Monane mopane tro'ma hu'nea Marerisa Anumzantega nagra huvempage hunte'noankina,
23 pé, èmi kì yóò mú láti fọ́nrán òwú títí dé okùn bàtà, àti pé, èmi kí yóò mú ohun kan tí ṣe tìrẹ, kí ìwọ kí ó má ba à wí pé, ‘Mo sọ Abramu di ọlọ́rọ̀.’
ru kagra nehunka Abramuna nagra hugeno feno nera mani'ne hunka hu'zanku nagra kukena hati nofiro, agia anomofo nofira, e'oritfa hugahue.
24 Èmi kì yóò gba ohunkóhun yàtọ̀ sí ohun tí àwọn ọkùnrin mi ti jẹ́, ṣùgbọ́n fi ìpín fún àwọn ọkùnrin tí ó bá mi lọ, Aneri, Eṣkolu àti Mamre. Jẹ́ kí wọn kí ó gba ìpín wọn.”
Nagrani'a mago'zana e'orisoanagi, vahe'ni'amo'zama ko'ma ne'zama ne'nazareke mesie. Hanki nagranema hate'ma vu'namokizmi atrege'za Aneriki, Eskoliki, Mamreki hu'za mago'a zana zamagra'a eriho.

< Genesis 14 >